Home Posts tagged Government College
Yoruba

Àwọn akẹ́kọ wọlé sẹ́nu ẹ̀kọ́ lẹ́yìn ìsimi ọlọ́jọ́gbọọrọ

Àwọn iléékọ alákọbẹ̀rẹ̀ àti girama tó jẹ́ taládani àti tìjọba nípinlẹ̀ Ọyọ wọlé padà fún sáà ètò ẹ̀kọ́ tuntun lẹ́yìn ìsinmi ọlọ́sẹ̀ mẹ́fà. Àwọn akọ̀ròyìn wa tí wọ́n lọ káakiri ìlú Ìbàdàn láarọ òní, jábọ̀ pé, láti bí aago méje láarọ òní ni wọ́n ti ńríì àwọn akẹ́kọ na tí wan ń lọ sílèwé wọn. […]Continue Reading