Home Posts tagged Iroyin
News Yoruba

Àwọn tóní àrùn kòkòrò HIV lára ńbèrè fún rírí ìtọ́jú gbà lái nira.

Àwọn tó fẹ́ gba ìtọ́jú kúrò lọ́wọ́ àrùn kókóró HIV nílèwòsàn ìjọba Heart to Heart nílu ọ̀yọ́ ńfẹ́ kí àmúbgòrò débá ètò ìgbáyégbádùn èyí tí ẹ̀ka tikise tìjọba gbé kalẹ̀, láti lèjẹ́ kí wọ́n lè borí ìpèníjà ètò ọrọ ajé tó ń bá ill yí fínra. Lára àwọn tó ní àrùn yí tó bá akọ̀ròyìn […]Continue Reading
News Yoruba

Ìjọba àpapọ̀ ńfẹ́ àtìlẹ́yìn àwọn orílẹ̀ èdè tó ti gòkè lórí fífi òpin sí ìgbésùnmọ̀mì

Alákoso fọ́rọ̀ ìròyìn àti àsà, Àlhájì Lai Mohammed ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn ilẹ̀ tóti gòkè àgbà láti se àtìlẹ́yìn fún orílẹ̀èdè Nàijírìa pẹ̀lú àwọn irinsẹ́ tó yẹ láti lè wọ̀ yája pẹ̀lú ìgbésùnmọ̀mí. Ó rawọ́ ẹ̀bẹ̀ yí lásìkò tó se àbẹ̀wò ẹkúsẹ́ ńbẹun sí Gómìnà Samuel Ortom nílèjọba tó wà ní Markurdi. Àlhájì Muhammed sọ […]Continue Reading