News Yoruba

Alakoso keji feto idaleese sile, eto okoowo ati oro aje lorileede yi Ambassador, Marian Katagum ti tenumo igbiyanju isejoba Aare Buhari lori atileyin sise fawon akanda eda lorileede yi.

Arabinrin Katagum siso loju oro yi lasiko to n gbalejo asoju egbe awon obinrin to je akanda eda, eyiti akowe egbe naa nile yi Mary Musa saaju mu.

Alakoso na salaye wipe ijoba to wa loke yi ko fowo yepere mu ofo awon akanda eda, leyi to mu ki won se idasile ajo kan ti yoo maa ri si igbaye gbadun won.

O soo di mimo pe, eredi ajo na ni lati le maa wa ojutu si ipenija yoowu ti won ba a koju nipase, eto ati liana tijoba nse.

Saaju ni akowe egbe naa, to tun je asaaju ile to se abewo wi pe won gunle abewo naa fun ajosepo pelu ileese to n ri si idase sile ati eto okoowo loro ati le maa koo awon akanda eda ni ise owo ati gbigba si ise laaye to ba si sile pelu awon anfani mii.

Babatunde Salaudeen

Yoruba

Ìjọba àpapọ̀ ti kéde mímú àtúnse tó gbọgbọ́n bá àwọn tó ti fara káaká ìwà ìfipábánilòpọ̀ lórílẹ̀èdè yíì.

Alákoso kejì fọ́rọ̀ ilésẹ̀ okòòwò àti ìdókoowò Arábìnrin Mariam Katagum kéde èyí nílu Abuja.

Ó sọpé, ilésẹ̀ náà nípasẹ̀ àwọn àjọ tówà lábẹ́ rẹ̀ yóò sàtìlkyìn tóní tumọ̀ fáwọn tó ti fara-kásá ìwà ìfipábánilòpọ̀ ọ̀hún, nípa kíkọ́wọn nísẹ́ ọwọ́, rírówọn lágbára àti dídáwọn lóokoowòo.

Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ igbákejì ọ̀gá tó wà fọ́rọ̀ àbùdá lákọ-lábo nílésẹ́ náà, arábìnrin Achinam Fidel sọpé pàtàkì ẹ̀ka náà níì láti se kóríyá fáwọn obìnrin nídi kíkópa nínú ìdáskajésílẹ̀, okòowò tó ti mọ ẹ̀ka ìjọba gbogbo.

Net/Elizabeth Idogbe