Home Posts tagged Niyi Dahunsi
Yoruba

Onímọ̀ bèèrè fún ìkọ́sẹ́mọsẹ́ nídi ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́

Wọ́n ti gbàwọn tóngbóhùn sáfẹ́fẹ́ látorí ẹ̀rọ ayélujára àtàwọn olùdásílẹ̀ rẹ̀ níyànjú láti jẹ́ akọ́sẹ́mọsẹ́ nídi isẹ́ tíwọ́n yàn láayo. Alájutó àgbà ilé-isẹ́ ẹlẹ́rọ amìnlújìnjìn Premier tó wà nílu ìbàdàn, Ẹniọ̀wọ̀ Niyi Dahunsi ló gbọ̀rọ̀ àmọ̀ràn yíì kalẹ̀, lákokò tó ń gbéwe àpilẹ̀kọ kan kalẹ̀ níbi ayẹyẹ àkọ́kọ́ ilé-isẹ́ Radio orí ẹ̀rọ ayélujára, Maranatha. Ẹniọ̀wọ̀ […]Continue Reading