Àjọ àbò ara ẹni láàbò ìlú, NSCDC, ti fàwọn òsìsẹ́ àjọ náà ẹgbẹ̀rúnméjìlélẹ́gbẹ̀rin sọwọ́, fún ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ tí yóò wáyé lọ́jọ́ àbámẹ̀ta ọjọ́ kejìlélógún osù larun ọdún yíì nípinlẹ̀ ọ̀yọ́. Ọga àgbà àjọ NSCDC nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ogbẹ́ni Iskilu Akinsanya sọ èyí lólú-ìlú ilésẹ́ náà, Agodi Continue Reading
Ajo eleto idibo ipinle Oyo, OYSIEC ti sun eto idibo ijoba ibile si ojo kejilelogun soun karun odun yi. Alaga ajo OYSIEC, Oloye Isiaka Olagunju lo fi ikede naa sita lasiko abewo to se si ajo to n ti si idagbasoke awon agbe, OYSADEP, eyi to wa ni Moore Plantation, Apata, Ibadan. Oloye Olagunju tenumo […]Continue Reading