Home Posts tagged Femi Akande
Yoruba

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọsun, Dáwọn Elẹ́wọ̀n Mọ́kànlá Sílẹ̀.

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀sun, ọ̀gbẹ́ni Adegboyega Oyetọla, ti síjú áànu wo àwọn ẹlẹ́wọ̀n mọ́kànlá tó wá láwọn ibùdó àtúnse ìlú Ilésà àti Ilé-Ifẹ, tó sì dáwọn sílẹ̀. Gómìnà Oyetọla tó sanwó ìtanràn àwọn ẹlẹ́wọ̀n mọ́kànla náà lákokò àyẹ̀wò tó gbópọn lórí ẹ̀sùn wọn, sọ pé, ìgbésẹ̀ náà wáyé láti mú àdínkù Continue Reading