Ètò ìkẹ́kọ ti bẹ̀rẹ̀ láwọn iléèwe ìjọba àti aládani tó wà nígbogro ìlú ìbàdàn. Akọ̀ròyìn Radio Nigeria tó lọ káàkiri jábọ̀ wí pé àwọn akẹ́kọ ti péjú sọ́gbà iléèwe wọn láàrọ òní pẹ̀lú isẹ́ ìmọ́tótó àyíká iléèwe wọn fún ìkẹ́kọ sáà tuntun. Ó sàkíyèsi wípé ní iléèwe Girama Ọba Akinbiyi tó wà ní Continue Reading
Yoruba News
Weekend Treat
Trending Now
Recent Posts
Categories
Archives
iframe: google.com, pub-5160901092443552, DIRECT, f08c47fec0942fa0
This is the head of your page
This is the body of your page.