Home Posts tagged Nàijírìa
News Yoruba

Orílẹ̀èdè Nàijírìa Fọwọ́sopọ̀ Pẹ̀lú Àwọn Alámulegbe Láti Gbógunti Ìgbésùnmọ̀mí.

Olórí ọmọ ológun Ibrahim Attahiru, sọpé àfojúsùn òhun ni tiridájúpé òpin débá ìwà ìgbésùmọ̀mí kóun gbogbo sì padà bọ̀ sípò lápá ìlàa-oorun ilẹ̀ yíì àtorílédé Nàijírìa lápapọ̀. Ọgagun àgbà Attahiru sọpé ikọ̀ ọmọlóju yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn ikọ̀ ọmọlógun Camaroon àti Chaad nídi fífòpin sí Continue Reading
News Yoruba

Ìgbìmọ̀ Gómìnà nílẹ̀ Nàijírìa sàlàyé ọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn kíkó ǹkan ìrànwọ́ pamọ́ lọ́nà àitọ́.

Àwọn Gómìnà nípinlẹ̀ mẹ́rìn dín lógún lábẹ́ àsía ìgbìmọ̀ nílẹ̀ Nàijírìa, ni wọ́n ti sọpé àwọn kokoo, àwọn ǹkan ìrọ̀rùn tó wà fún àwọn tó kudiẹ káto fún láwùjọ pamọ́ lásìkò tí fífi òpin sí ìtànkálẹ̀ àrùn covid-19 le dandan.  Àwọn Gómìnà ló sọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ nínú àtẹ̀jáde èyí tí olórí lẹ́ka tón mójútó […]Continue Reading
Yoruba

Ilẹ̀ Nàijírìa àti Chad sọ̀rọ̀pọ̀ lórí isẹ́ àgbẹ̀

Orólẹ̀èdè wa Nàijírìa, ilẹ̀ olóminira Niger àti orílẹ̀èdè Chad ti ńsisẹ́ lórí àkànse ètò láti fi se àtúnse ibùdó adágún odò Chad, kí ètò ìgbáyégbádùn ba lè wà fáwọn èèyàn tó wà lágbègbè adágún odò na. Ọga àgbà àjọ kan tí wọ́n ń pè ní National Agency for the great green wall, ọ̀mọ̀wé Bukar Hassan […]Continue Reading