Àjọ tó rísí ètò ìlera nípinll Èkó sọpé, ohun ti ńgbé ìgbésẹ̀ láti sàfikún àwọn olùgbé tóòtóò milliọnu mẹ́ta sínú ìlànà ètò ìlera adójútófo ti ìforúkọsílẹ̀ náà yóò sì wáyé lárin ọdún kan. Alákoso àgbà fájọ ọ̀hún Dókítà Emmanuẹla Zamba, sọ èyí di mímọ̀ níbi ìpàdé ètò ìlanilọ́yẹ̀ àwọn èèyàn ẹsẹ Continue Reading
Ijoba ipinle Eko ti so pee to iranwo eyi ti banki Agbaye gbe kale lati mu kagbega deba akowo ati igbaye gbadun araalu, ni yo se atileyin fun ise akanse kilo opopona to wo oko to le ni ibuso agbegbe oko merin otooto. Alakoso feto ogbin nipinle Eko, Arabinrin Abisola Olusanya, lo je koro yi […]Continue Reading
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti sọpé gbogbo òpópónà àti afárá èyí tí wọ́n ńkọ́ lọ́wọ́ ládugbò Apapa ni yo jẹ píparí nínú osù kẹwa ọdún tawàyí. Gómìnà Babajide Sanwo-olu ló sọ̀rọ̀ ìdánilójú yi lásìkò tó se àbẹ̀wò láti mọ ibi tísẹ́ dé dúró lágbègbè náà, n’ípinlẹ̀ Èkó. Gómìnà Sanwo-olu, sọpé súnkẹrẹ f’àkẹrẹ ọkọ̀, tón f’ojúmọ́ faye […]Continue Reading
Gomina Ipinle Eko, Babajide Sanwo-Olu ti ro awon olugbe ilu Eko lati se suuru lori isoro ti won yio foju wina re laarin osu mega ti won fe fi ti abala kan afara 3rd Mainland bere lati oni lo. O soro yi lasiko ti o ngbalejo oga ajo eso oju popo FRSC tuntun nipinle Eko, […]Continue Reading