Àrẹ Muhammade Buhari ti sọ pé àmúgbòrò yo de bá ìgbáyé gbádùn àwọn èyàn nílẹ̀ Nàijírìa, bẹ̀rẹ̀ nípa ìpèsè ètò àbò tó múnádóko.

Nílu Maiduguri, l’afin Shehu ti Borno, ni àrẹ ti sọ̀rọ̀ ìdánilójú yi .

Àrẹ ẹni tó ń se àbẹ̀wò ẹnu isẹ́ ọlọ́jọ́ kan sípinlẹ̀ Borno, ló ti kọ́kọ́ se ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú okọ̀ ológun tó wà lágbègbè ọ̀hún.

Óní ìpinu òun láti sin àwọn èyàn orílẹ̀èdè yí, ló wà tatara ifẹ̀ tí wọ́n fihàn sí, bẹ lótún gbóríyìn fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno lórí akitiyan rẹ̀ láti mú ìdàgbàsókè bá ìpínlẹ̀ náà láiwo ìpèníjà lórí àbò tí wọ́n ńlà kọjá.

Nínú ọ̀rọ̀ Shehu tílù Borno, àlhájì Abubakar El-kanemi, dúpẹ́ lọ́wọ́ àrẹ lórí idahun sí ìbere àwọn èyàn ìpínlẹ̀ náà, pẹ̀lú àtọ́kasí pé ètò àbò tin rẹsẹ̀ walẹ̀ sí nípinlẹ̀ ọ̀hún.

Ọlọlade Afọnja

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *