O se Pataki ki ajosepo was laarin ijoba ni gbogbo eka ati ileese aladani lati mu ki amugbooro de ba nini anfani si eto ilera to koju owo. Igbakeji Aare, Ojogbon Yemi Osinbajo lo soro yi lasiko to n siso loju ipade apero eto ilera alabode kan nilu Abuja. Ojogbon Osinbajo tenumo pe ibasepo laarin Continue Reading
Yoruba
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti pàrọwà fáwọn onímọ̀tó láti ní ẹ̀mí ìgbọ́raẹniyé lórí bí wọ́n tise ńgberò àti bẹ́ẹ̀rẹ̀ síì gbowó padà lẹ́nu ìloro Lẹ́kkí. Alákoso fọ́rọ̀ ìròyìn nípinlẹ̀ Èkó ọ̀gbẹ́ni Gbenga Ọmọtọsọ ló pàrọwà yí nílu Èkó. Ọgbẹni Ọmọtọsọ tẹnumọ́ ìdí tí àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Èkó fi gbọdọ̀ máà fojú áànu wo àwọn òsìsẹ́ ẹnu […]Continue Reading
Ọkọ̀ agbepo kan tó kún fún epo bẹntirol ti da ẹrù rẹ̀ nù lágbègbè Dangote, tó wà ní ìdígba Ilọra lópopónà másọsẹ̀ ọ̀yọ́ sí ìbàdàn, èyítí ó ti fi àwọn awakọ̀ àti olugbé ibẹ̀ sínú ewu. Akọ̀ròyìn ilésẹ́ Radio Nigeria ríì gbọ́ wípé awakọ̀ epo nà ni wọ́n ti gbé lọ sí iléwòsàn lásìkò tó […]Continue Reading
Ẹgbẹ́ àwọn akọ́sẹ́mọsẹ́ lórí adójútófo nílẹ̀ yí CIIN ẹ̀ka tìpińlẹ̀ ọ̀yọ́ ti búra fún àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ tuntun. Ètò yí tó wáyé níbi ayẹyẹ ìfàmìẹ̀yẹ dáni lọ́lá àti ìgbaniwọlé ọlọ́lọọdún wọn tó wáyé nílu ìbàdàn ni wọ́n ti búra fún ọ̀gbẹ́ni Ọladeji Akinọla gẹ́gẹ́bí alága àti àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ mẹ́jọ min tí wọn yio tukọ̀ […]Continue Reading
Alága ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàijírìa lókèèrè, ẹ̀ka ti orílẹ̀ èdè Hungary, ọ̀mọ̀wé Hussaini Argungun ti bèèrè fún àtìlẹyìn ilésẹ́ ìjọba àpapọ̀ fọ́rọ̀ amujo ìjàmbá àti mímú ìdẹ̀rùn bá ará ìlú lórí àwọn akẹ́kọ ọmọ olẹ̀yí tí wọ́n sá kúrò ní Ukraine kí wọ́n báà le dúró ní Hungary. Ọmọwe Argungun ẹnití ó ńbá ilé […]Continue Reading
Àbá òfin láti sàyípadà ilé ẹ̀kọ́ gíga ìmọ̀ ẹ̀rọ Ládòkè Akintọla, LAUTECH, sí ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n ti ńkọ́ ìmọ̀ gbogbogbò ni wọ́n ti kà fún ìgbà kejì nílé ìgbìmọ̀ asòfin Ìpínlẹ́ ọ̀yọ́. Èyí ló jẹ́ nítorí ìwé kan tí Gómìnà Seyi Makinde fi sọwọ́ sílé ìgbìmọ̀ asòfin tí adarí ilé, ọ̀gbẹ́ni Adebọ Ogundoyin kà […]Continue Reading
Àjọ ẹ̀sọ́ ojú pópó, FRSC, ti ní lílo ìlànà ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé tí múkí ọwọ́ isẹ́ túbọ̀ yá kánkán àti jáfáfá síì léyití ó ti jẹ́kí àdínkù dé bá àwọn ìjàmbá ojú pópó. Ọga àgbà àjọ FRSC, ọ̀mọ̀wé Boboye Oyeyẹmi ló sọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ níbi ìdánilẹ́kọ kan tó wáyé nílu Abuja. Ọmọwe Oyeyẹmi wá […]Continue Reading
Àarẹ orílẹ̀dè yíì, Muhammadu Buhari ti sọ́ọ̀di mímọ̀ pé, ìsèjọba òun ti n wójùtú sọ́rọ̀ ilégbe fáwọn ọmọ orílẹ̀dè yíì, papajùlọ àwọn tó ń gbé láwọn ìlú ńlánlá. Lákokò tó ń sèfilọ́lẹ̀ àwọn isẹ́ àkànse ilégbe, abala àkọ́kọ́ nílu Òsogbo, tí sólùlú ìpínlẹ̀ Ọsun, áàrẹ sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà. Áàrẹ Buhari ẹnití alákoso fọ́rs abẹ́lé, […]Continue Reading
Agbẹjọ́rò kan, ọ̀mọ̀wé Kazeem Olaniyan ti gbàwọn ọmọ ilé- ìgbìmọ̀ asòfin àpapọ̀ níyànjú láti tọwọ́ òfin tóníse pẹ̀lú káwọn asojú kan bo somun bọnú àtúnse ìwé òfin tónlọ lọ́wọ́. Ọmọwe Ọlaniyan tótún jẹ́ olúkọ̀ lẹ́ka tíwọ́n tin kọ́ nípa ìmọ̀ òfin nílé ẹ̀kọ́ gíga fásitì ìbàdàn ló gbọ̀rọ̀ àmọ̀ràn yíì kalẹ̀ lákokò tó ń kópa […]Continue Reading
Ona gbogbo to dari si gbongan isembaye ilu Ibadan tii se Mapo lawon to ba fe gba ibe koja gbodo wa ibo miin gba nipa bi Olubadan Keilelogoji (42), oba Lekan Balogun yoo se maa gba ade lola. Eyi lo jeyo laodo ajo to n ri si igbokegbodo oju opop nipinle Oyo OYRTMA ninu atejade […]Continue Reading
Awon omo ile Nigeria ti kesi ijoba apapo ati ajo elepo robi NNPC pelu gbogbo awon toro kan leka epo robi ati afefe gaasi pe ki won rii daju pe epo petirolu po yannturu fun lilo araalu. Won foju oro yi lede lasiko ti akoroyin Radio Nigeria n to pinpin ibi ti inkan de duro […]Continue Reading
Aare Orileede yi, Mohaamadu Buhari ti fi aidunu re han lori bawon iko olote kan se lo dode awon eso alaabo oru, eyi to yo ri si biwon se sekupa die lara won nijoba ibile Sakaba Wasagu nipinle Kebbi. Eyi lo jeyo ninu atejade kan toluranlowo Pataki fun Aare loro iroyin ati ibaraeni soro, Mallam […]Continue Reading
Oludari ajo abo ara eni laabo ile, Nigeria Security and Civil Defence Corps, NSCDC, eka tipinle Oyo, Ogbeni Michael Adaralewa ti sefi lole iko kan ti yoo maa gbogun ti awon ayederu eso alaabo. Iko amuseya naa, niwon mu won lati eka aladani tiwon je akosemose osise, alaabo nile yi, eka tipinle Oyo. Nibi ifilole […]Continue Reading
Ijoba apapo si so pe oun koni faye gba gbigba awon eeyan nile Nigeria gegebi ajagun oke okun lo si ile Ukraine. Gegebi atejade eyi ti agbenuso ti alakoso foro okeere, Francisca Omayuli fowosi ijoba lo ti n ni ajosopo pelu ile Ukraine lati le da irufe igbese be duro. Atejade naa lo waye leyin […]Continue Reading
Awon toro eko gberu ti tenumo mimu eto eko omobinrin ni dandan. Won soro amoran yi lasiko idanilekmo lati fi samin agbega omowe Morufat Balogun, tile eko giga versity Ibadan si ojogbon nipa Genetics. Okan lara awon to gbe idanileko kale ti se olukoni lati ile eko giga Versity Ipinle Eko, LASU, Omowe Khadijat Shobowale […]Continue Reading
Ile Igbimo Asofin ile Nigeria ti fun awon ijoba ibile nile yi lominira eto enawo jakejado ile Nigeria pelu bo se pari agbeyewo ofin odun 1999. Awon asofin ile igbimo asofin mejeeji ni won dibo lori aba ofin mejidinlaadorin pelu bi won se foowo si awon kan ti won si satako sawon min. Ninu ibo […]Continue Reading
Oga agba yanyan fun ile ise Olopa ile Nigeria, Ogbeni Usman Baba ti sekilo fawon osise olopa lati jina si lilo anfani awon ibudo ayewo oju ona ati didekun awon odaran fun gbigba owo abetele. Ogbeni Baba to sekilo naa loluu ile ise olopa nilu Abuja fun awon logaloga agbegbe ati elekunjekun to fimo awon […]Continue Reading
Awon olugbe ilu’Badan ti kesi ijoba lati wojutu si owongogo epo pentrol to n faalee. Won soro yi lasiko ti won n ba akoroyin ileese Radio Nigeria to n topinpin isele owongogo epo naa.Lara awon olugbe ohun, koroju si bawon ile epo se n ta oja, laarin igba naira si igba le ladota naira, eyi […]Continue Reading
Lola ode yi, ireti w ape ijoba apapo yo bere si ni ko awon eeyan ile Nigeria to wa ninu rogbodiyan laarin Ukraine ati Russia wale. Alakoso foro ile okere, Ogbeni Geaffrey Onyeama lo je koro yi di mimo lasiko ipade po pelu adari ile asofin agba, Ogbeni Femi Gbajabiamila. Ogbeni Onyeama so pe gbigbe […]Continue Reading
Lona ati wojutu si igbese iyanselodi, eyi tegbe awon osise lawon ile-eko giga fasity, Ile yii, ASUU, gunle egbe naa ati Ijoba Apapo orilede yii ti setan lati se ipade Lori iyanselodi ohun. A o ranti pe, ojo aje tokoja legbe ASUU gunle iyanselodi olosu kan, eyi tiwon fi n kesijoba lati dahunsi ohun tiwon […]Continue Reading
Iyawo Gomina Ipinle Oyo, Arabinrin Tamunominimi Makinde ti kesi awon omo ile Nigeria pe ki won dide atileyin fawon obinrin to lugbadi ijamba lasiko abe dida fomobirin. Arabinrin Makinde soro imoran yi lasiko eto ayajo fifopin si abe dida fomobinrin fun todun yi. Iyawo Gomina, eni ti alakoso akanse ise nipinle Oyo, Arabinrin Fausat Sanni […]Continue Reading
Ajo elepo robi nile yi ti soo di mimo wipe won ti da oko oju omi akeru nla marun to gbe eroja epo petrol to ni ethano laden marun pada, nigba ti won kefin pe eroja epo petirolu na ko koju osuwon. Oludari agba ajo NNPC, Mebe Kyari lo foju oro yi lede lasiko to […]Continue Reading
Ilese to n risi iwole wode nile yii, NIS ti kede pe awon ti si oju opo eto iforukosile fun gbigba iwe irinna atowo sisan pada. Eyi lo jeyo ninu atejade kan tagbemuso ibudo naa, Ogbeni Amos Okpu fisita nilu Abuja. Oludari agba patapata fun Ajo ton risi iwole wode nile yii, Ogbeni Muhammadu Babandede, salaye […]Continue Reading
Olubadan tuntun omowe Lekan Balogun ti tewo gba iwe iyansipo gegebi Olubadan ile Ibadan. Iwe iyansipo naa ni akowe agba fun ileese to wa for ijoba ibile ati oye jije nipinle Oyo, Omowe Bashir Olanrewaju fowo si. Iiwe iyansipo naa ni Alaga Ijoba ibile Guusu Ilaaoorun Ibadan, Ogbeni Emmanuel Alawode mu lo sile Oluban tuntun […]Continue Reading
Egbe awon oluko ile eko giga fasiti nile yi, ASUU ti soo di mimo pe ajo to n seto idanwo ati wole sile eko giga (JAMB) lo leto lati maa set igbaniwole sawon ile eko giga. Ninu atejade, eyi ti aare egbe ASUU, Ojogbon Emmanuel Osodeke fi sita lo ti salaye wipe igbese ajo JAMB […]Continue Reading