Home Archive by category News (Page 454)

News

News Yoruba

Gómìnà Seyi Makinde Sèlérí Ìpèsè Irinsẹ́ Fáwọn Àjọ Elétò Áàbò Nípinlẹ̀ Ọ̀yọ́

ómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde ti sèlérí àti ró àwọn àjọ elétò áàbò lágbára síì láti léè sisẹ́ dójú àmìn láti léè jẹ́kí àláàfìa jọba nípinlẹ̀ yi. Ó sèlérí ọ̀rọ̀ yí níbi ìsìn ìdúpẹ́ láti fi sàmì ayẹyẹ ọdún méjì rẹ̀ lórí ipò Gómìnà èyítí ó wáyé nínú ìjọ Peteru mímọ́ tó wá […]Continue Reading
News Yoruba

Àjọ NSCDC Bèèrè Àtìlẹyìn F’awọn Asọgbo Ọba

Àjọ ààbò ara ẹni láàbò ìlú NSCDC, ti ńbèèrè fún àtìlẹyin àwọn ará ìlú láti léè túbọ̀ síse wọn bíì isẹ́. Ọga àgbà àjọ NSCDC, nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbẹ́ni Iskilu Akinsanya ló sọ̀ro yí lásìkò tó sàbẹ̀wò isọwọ síse àwọn asogbo ọba láti ìgbàtí wọ́n ti sèfilọ́lẹ̀ rẹ̀ nípinlẹ̀ ọ̀yọ́ tó wáyé ní olú ilé isẹ́ […]Continue Reading
News Yoruba

Àjọ NITDA sèkìlọ̀ lórí ìdúnkokò tuntun orí ẹ̀rọ ayélujára.

Àjọ tó ńrísí ọ̀rọ̀, ìdàgbàsókè ìmọ̀ ẹ̀rọ nílẹ̀ yí NITDA ti kìlọ̀ lórí ìdúnkokò tuntun lórí ẹ̀rọ ayélujára tó ńlọ́wọ́ ìfìwéránsẹ́ lọ́nà ìgbàlódé email, nínú láti ọwọ́ àwọn ọmọ ilẹ̀ Russia kan tí wọ́n ńpè ní NOBELIUM. Ìkìlọ̀ yí ló wá nínú àtẹ̀jáde ti ẹniti ó ńrísí ọ̀rọ̀ tó kàn ará ìlú nínú àjọ NITDA, […]Continue Reading
Politics

Ayade Sacks 4 Commissioners, Others

Cross River State Governor, Ben Ayade, has sacked four commissioners from his cabinet. This was contained in a statement issued by Special Adviser to the Governor on Media and Publicity, Mr Christian Ita in Calabar. According to the Statement, those affected by the sack are commissioners are Mike Usibe (New City Development), Rita Ayim (Women […]Continue Reading
Politics

Police Deny Officer Attacked Omoyele Sowore

The Federal Capital Territory Police Command has denied that any of its officers shot Mr. Omoyele Sowore this morning. This is contained in a statement by spokesperson for the command, Mariam Yusuf. The statement debunks the viral message in some sections of the social media purporting that Sowore was shot by a female Assistant Commissioner of […]Continue Reading
Crime

Police Confirm Murder Of Ibadan Businessman

The Police Command in Oyo State on Sunday confirmed the killing of a 51-year-old Ibadan businessman, Maduabuchi Owuamanam, by gunmen. Owuamanam was murdered on Saturday at a relaxation spot at Oremeji Mokola area of Ibadan by yet-to-be identified gunmen. The Command’s Public Relations Officer, PPRO, DSP Adewale Osifeso, confirmed the incident in a statement made […]Continue Reading
Foreign Politics

ECOWAS Suspends Mali Over Coup

West African regional bloc ECOWAS on Sunday suspended Mali’s membership in response to last week’s coup and urged authorities to adhere to a timetable for a return to democracy. This was the decision after the Leaders of the 15-member Economic Community of West African States held an emergency summit in Ghana, the capital of Accra […]Continue Reading
Education

ASUU Gets New President

After he had successfully headed the Academic Staff Union of Universities, ASUU, for some years, Professor Biodun Ogunyemi, bowed out last week. He created a way for Professor Victor Emmanuel Osodeke of the Michael Okpara University of Agriculture, Umudike in Abia State to emerge, as the new President of the association. The election took place […]Continue Reading