Home Archive by category Yoruba

Yoruba

Yoruba

Ida Emi Ara Eni Legbodo: Ona Abayo

Temitope Bolugbe Ida emi ara eni legbodo ti di gbomo gbomo laarin awọn ọdọ ode òní, o sí je ọnà kán tó ya sí ikú. Gege bí àjọ eleto ìlera l’agbaye (WHO) se sọ, o jẹ ọnà kàn gbòógì tó n ṣokunfa ikú láàrín àwọn ọmọ ọdún marundinlogun sí ọmọ ọdún mokandilogbon l’agbaye ní ọdún […]Continue Reading
Yoruba

Ìjọba ìpínlè Ogun sàgbékalè ètò ayẹwo ojú ọ̀fẹ́ fáwọn onimoto

Àjọ ton mojuto idagbasoke eto ìlera alabode nipinle Ogun pẹ̀lú ifowosowopo ìgbìmò tó ń risi ọrọ ìlera ojú nipinle náà tí sàgbékalè ètò ayẹwo ojú lofe fáwọn onimoto, ero àtàwọn aladani láwọn ibùdóko jákèjádò ìpínlè náà gẹ́gẹ́bí ara eto ton sàmìń ayajo ọjọ́ iriran tóko lọ́dún yi. Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí àkòrí todun yi, […]Continue Reading
Yoruba

Ègbé ASUU Sewele Iyanselòdi Olosu Mẹ́jọ

Ègbé olùkọ́ láwọn ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì nileyi, ASUU tí sewele iyanselòdi olosu mejo rẹ pẹ̀lú àwọn afẹnukò ìlànà kan. Alága ẹgbẹ́ náà fún olú ìlú wa Abuja, Ojogbon Kasimio Umar ló fìdí ọ̀rọ̀ náà múlè fáwọn akoroyin nilu Abuja.  Ègbé náà pinnu láti fòpin sí iyanselòdi ohun lásìkò ìpàdé àwọn adarí tó bẹ̀rẹ̀ lalẹ àná […]Continue Reading
Yoruba

Egbé àwon òsìsé NLC sí n tèsíwájú lenu ìwóde olojo méjì rè to gùnlé yíka orileede.

Ní itesiwaju ètò ìwóde tégbé òsìsé NLC gùnlé yíka orilede Nigeria, èyí tó ti wo ojó kejì bayii, Egbé náà atawon akegbé rè ti wode yíká ìlú Abuja loni.  Ìròyìn sopé, lati nnkan bi ago méje òwúrò Òní lawon òsìsé ti peju- pese si unity Fountain feto ìwóde náà. Níbáyìnáá, ètò àbò ti gbóná girigiri, […]Continue Reading
Yoruba

Ètò ìwóde Egbé àwon òsìsé, NLC, wáyé yíká àwon ìpínlè ílè yí

Ètò ìwóde Egbé àwon òsìsé NLC ti wáyé yíká àwon ìpínlè lorilede yí.  Ètò ìwóde náà tegbe àwon òsìsé gùnlé lo wáyé láti fi sàtìleyìn fun ìyansélódì Egbé ASUU to nlo lówó, tíwón si tún fi n sàfihàn àìdùnú lori owó tíjoba àpapò mórò ìyansélódì olósè méjìlá Egbé ASUU náà. Àbò ìròyìn láti àwon ìpínlè […]Continue Reading
Yoruba

Agbejórò Àgbà Nílè Yí, Korin Re Aséyìn Tìlú Ìséyìn To Wàjà

Baamòfin fun agbègbè Òkè- Ògùn, títún se, Agbejórò Àgbà nílè yí, Olóyè Jelili Owonikoko, ti sàpéjúwe Aséyìn tìlú ìséyìn to wàjà, Oba Abdulganiyu Adekunle, gégé bí  olórí tí gbogbo àwon èèyàn bòwò fun , tíwón si tún fenípò pelu, fún gbogbo àkókò to Lori àpèrè àwon baba ñla rè. Nínú ìwé ìbánikédùn tó ko , […]Continue Reading
Yoruba

Bí Igba Làwọn Akẹ́kọ́ọ̀ tó Jóko Sèdánwò Igbaniwọlé Sáwọn Iléwé Girama Nípinlẹ̀ Oyọ́

Bí igba ọdún dìẹ làwọn akẹ́kọ́ọ̀ ilé-ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ tó jóko sèdáwò àyẹ̀wò bákẹ̀kọ́ kan se gbéwọ̀n sí láti wọ ile ẹ̀kọ́ girama nípinlẹ̀ ọ̀yọ́. Alákoso fétò ẹ̀kọ́ ìmọ̀ sáyẹ̀nsì àti tìmọ̀ ẹ̀rọ nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbẹ́ni Rahman Abdul-Raheem ló kéde bẹ́ẹ̀ nílu Ìbàdàn, bẹ́ẹ̀ lósì fi ìdùnú rẹ̀ hàn lórí, bẹ́tò ìdánwò náà fún tọdún 2022 […]Continue Reading
Yoruba

Àwọn àláàjì ilẹ̀ yí ti bẹ̀rẹ̀ síì níì padà wale

Wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí níì gbé àwọn aláàjì láti orílẹ̀ èdè Saudi Arabia padà wa sílẹ̀. Báàlù pẹ̀lú nọ́mbà ìmínimọ̀ xy7002 tó gbé àwọn aláàjì tó lé ní irinwó láti olú ìlú ilẹ̀ yí lọ gbéra kúrò ní pápá òfurufú ọba Abdulazeez tó wà ní Jeddah wá sí pápákọ̀ Nnamdi Azikwe nílẹ̀ yí. Alága àjọ […]Continue Reading
Yoruba

Àjọ INEC ti gbaradì fétò ìdìbò Gómìnà nípinlẹ̀ Ọsun

Àjọ elétò ìdìbò ilẹ̀ yí, INEC, ti pín àwọn ohun èèlò ìdìbò sáwọn ìjọba ìbílẹ̀ ọgbọ̀n ní ìpalẹ̀mọ́ fún ètò ìdìbò sípò Gómìnà tí yio wáyé nípinlẹ̀ Ọsun lọ́la. Pínpín àwọn ohun èèlò ìdìbò ọ̀hún ló wáyé ní ọ́fìsì INEC, tó wà l’ósogbo níbití àwọn asájú ẹgbẹ́ òsèlú, àwọn oníròyìn àti ònwòye ètò ìdìbò péjú […]Continue Reading
Yoruba

Biden Yio Sèpàdé Pọ̀ Pẹ̀lú Asáàjú Ilẹ̀ Palestine, Saudi Arabia

Àarẹ ilẹ̀ America, Joe Biden ni yio se pàdépọ̀ pẹ̀lú àwọn adarí ilẹ̀ Palestine tí wọ́n wà lágbègbè West Bank lóni sáàjú kó tó lọ síbi ìpàdé àpérò ni Saudi Arabia. Gẹ́gẹ́bí ohuntí àwọn ònwòye sọ, ó seese kí ǹkan lọ́ jái níbi ìpàdé náà pẹ̀lú Mahmoud Abbas nítorí gbúngbùngbún tó wà láàrin wọn pẹ̀lú […]Continue Reading
Yoruba

Àarẹ Buhari kí ikọ̀ Super Falcons kú oríìre àseyọrí wọn nínú ìdíje WAFCON

Àarẹ Muhammadu Buhari ti kí ikọ̀ agbágbbọ̀ọ̀lù Super Falcons kú oríìre àseyọrí wọn nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú ikọ̀ Indomitable Lioness ti Cameroon pẹ̀lú àmì ayò kan sí òdo nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpele kejì tó kángun sí àsekágbá níbi ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ adúláwọ̀ tàwọn Obìnrin tọdún 2022 tó ńlọ ní Morocco. Àtẹ̀jáde látọ̀dọ̀ amúgbálẹ́gbẹ àarẹ lórí […]Continue Reading
Yoruba

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọsun, Dáwọn Elẹ́wọ̀n Mọ́kànlá Sílẹ̀.

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀sun, ọ̀gbẹ́ni Adegboyega Oyetọla, ti síjú áànu wo àwọn ẹlẹ́wọ̀n mọ́kànlá tó wá láwọn ibùdó àtúnse ìlú Ilésà àti Ilé-Ifẹ, tó sì dáwọn sílẹ̀. Gómìnà Oyetọla tó sanwó ìtanràn àwọn ẹlẹ́wọ̀n mọ́kànla náà lákokò àyẹ̀wò tó gbópọn lórí ẹ̀sùn wọn, sọ pé, ìgbésẹ̀ náà wáyé láti mú àdínkù bá báwọn ibùdó àtúnse náà […]Continue Reading
Yoruba

Ìjọba Àpapọ̀ Sàwárí Egbẹ̀rún kan Àtàbọ́ Osise Pelu Ayederu Ìwé  Igbanisise

Ijọba àpapọ̀ ti sàwárí òsìsẹ́ tó lé ní ẹgbẹ̀rún kan àtàbọ́, tójẹ́ pé ìwé ìgbanisísẹ́ ayédèrú ni wọ́n lò láti darapọ̀ mọ́ isẹ́ ìjọba. Olórí òsìsẹ́ nílẹ̀ yí, ọ̀mọ̀wé Fọlasade Yẹmi-Ẹsan ló sọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ nílu Abuja. Ọmọwe Yẹmi-Ẹsan sọpé ó lé ní ẹgbẹ̀rún kan àwọn èyàn tí wọ́n sàwárí ní ẹ̀ka ilésẹ́ kan, […]Continue Reading
Yoruba

Ìjọba àpapọ̀ pè fún ìgbésẹ̀ fifòpin sí lílo ọmọdé nílòkulò

Ìjọba àpapọ̀ ti pè fún àmójútó tó péye láàrin àwọn tọ́rọ̀ kàn nídi àti fòpin sí lílo ọmọdé nílòkulò nílẹ̀ Nàijírìa. Akọ̀wé àgbà iléesẹ́ ìjọba àpapọ̀ tó wà fún ọ̀rọ̀ òsìsẹ́ àti ìgbanisísẹ́, Dókítà Yerima Peter-Tarfa ló pèpè yí nílu Abuja lásìkò ètò ìdánilẹ́kọ tó wáyé fáwọn olùdarí ẹkùn àti alámojútó láwọn ìpínlẹ̀ nípa ètò […]Continue Reading
Yoruba

Olúbàdàn t’ilẹ̀ ‘bàdàn sèkìlọ̀ fáwọn égúngún láti yàgò fún ìwà jàgídíjàgan lákokò ọdún wọn.

Olúbàdàn tilẹ̀ ìbàdàn ọba Lekan Balogun ti sìkìlọ̀ fáwọn atọ́kùn ègùngùn, àtàwọn tó fẹ́ báwọn kọwọ ọdún pé kí wọ́n yàgò fún jàgídíjàgan lásìkò ayẹyẹ ọdún ilẹ̀ ìbàdàn tí yóò bẹ̀rẹ̀ lósù tó n bọ̀. Ọba Balogun sàlàyé ọ̀rọ̀ yí lásìkò àbẹ̀wò alágbáà tíì se olórí àwọn egùngùn nílé olúbàdàn tó wà ní alárere. Ọba […]Continue Reading
Yoruba

Òjò sọsẹ́ nílu bàdàn

Òjò alágbára tó rọ̀ nílu’bàdàn lána òde yi ti ba àwọn ilégbe iléwe tófimọ́ òpó iná jẹ́. Akọ̀ròyìn ilésẹ́ Radio Nigeria tó tọpinpin ìsẹ̀lẹ̀ náà, jábọ̀ pé òrùlé àwọn ilégbe kan lágbugbò Agbowó àti orogún ni ìjì ọ̀hún gbé lọ. Yàtọ̀ fún àwọn ìgì tó wọ́lu ojú òpópónà, àwọn irinsẹ́ tón mú iná wọlé ilésẹ́ […]Continue Reading
Yoruba

Àwọn Ẹléri Jèhófà Sí Gbọ̀gàn Ìpàdé Wọn Padà

Àwọn ẹlẹ́ri Jèhófà nílẹ̀ yí àti káàkiri àgbáyé ni wọn yio si gbọ̀gàn ìpàdé wọn padà lọ́jọ́ ẹtì ọ̀sẹ̀ yí lẹ́yìn tí wọ́n ti gbéè tì padà fún bíì ọdún méjì níbamu pẹ̀lú ìlànà áàbò àti dènà ìtànkálẹ̀ àrùn covid 19. Àtẹ̀jáde látọ̀dọ̀ olú ile isẹ́ àwọn ẹlẹ́ri Jèhóvàh sọ wípé àkànseàsọyé ọlọ́gbọ̀n ìsẹ́jú tí […]Continue Reading
Yoruba

Ilésẹ́ Ìrìnà Ojúrin Nílẹ̀ Nàijírìa, NRC, Fòfinde Ìrìnà Láti Abuja Lọ Sí Kaduna

Ilésẹ́ tón rísí ìrìnà ojú irin ti fòfinde ìrìnà láti Abuja lọ sí Kaduna, tí kò sì ní gbèdéke. Ilésẹ́ náà ló jẹ́ kọ́rọ̀ yí di mímọ̀ nínú ọ̀rọ̀ tó fi síta lójú òpó abẹ́yẹ fò twitter rẹ̀ lóòrọ yi. Ó sọ pé ìfòfindè náà ló wáyé fún àwọn ìdí tí wọ́n kò lérò, tó […]Continue Reading
Yoruba

Ìjọba Àpapọ̀ Se Ìfilọ́lẹ̀ Ètò Ìdàgbàsókè Ọrọ̀ Ajé Láwọn Ìpínlẹ̀

Igbákejì Àrẹ, Yẹmi Ọsinbajo ti kéde ìdásílẹ̀ ètò ìdàgbàsókè mẹ́fà èyí tí ìjọba àpapọ̀ fẹ́ gùnlé láwọn lẹkun kọ̀kan nílẹ̀ yí, láti lè mú kí àgbéga débá ọrọ̀ ajé láwọn  ìpínlẹ̀. Igbákejì Àrẹ kédeyi lásìkò àpérò ilẹ̀ adúláwọ̀ níbi tí àtúntò fọ́dún 2022 yo ti wáyé nílu Abuja. Ọjọgbọn Ọsinbajo sọ fún àwọn akópa pé […]Continue Reading